Ajagungbalẹ yawọ Ketu- Ẹpẹ, ọpọ awọn eeyan ni wọn ṣe nijamba IROYIN OJUTOLE April 11, 2025 Titi di akoko ta a wa yii, ọpọ awọn eeyan ni wọn wa nile iwosan nibi ti wọn ti n gba itọju nitori bi wọn ṣe lawọn ajagungbalẹ ya... KAA SIWAJU
Alaga ijọba ibilẹ Mushin, Ọnarebu Bamgboye ni: Awọn ísẹ akanṣe ta a ṣe lo sọ wa di aayo awọn araalu IROYIN OJUTOLE March 28, 2025 Lara awọn ijọba ibilẹ to ti pẹ lorileede Naijiria nijọba ibilẹ Mus... KAA SIWAJU
Pẹlu owo tabua to n wọle sapo Eko, ìyà ṣi tun n jẹ awọn araalu - Gbadebo Rhodes Vivour IROYIN OJUTOLE March 18, 2025 Oludije fun ipo gomina nipinlẹ Eko labẹ asia ẹgbẹ oselu 'Labour Party' ni ọdun 2023 Gbadebo Rhodes-Vivour ti bu ẹnu atẹ ... KAA SIWAJU
A ti fi ti Jandor sarìkọgbọn, a ko ni i fun eeyan jagbajagba laaye lati dupo ninu ẹgbẹ wa mọ- Oloye Bọde George IROYIN OJUTOLE March 16, 2025 Baba wa, njẹ e le sọ fun wa ibi ti ẹgbẹ oṣelu PDP wa lakooko yii? Gbogbo eeyan naa lo n beere pe nibo ni ẹgbẹ a w... KAA SIWAJU
Wahala to sele nile igbimo asofin Eko laipe yii, ibanuje nla ni- Gbadebo Rhodes Vivor IROYIN OJUTOLE March 09, 2025 Gbajugbaja ni Ayaworan-ile Gbadebọ Rhodes-Vivour jẹ lagboole oṣelu lorileede Naijiria, paapaa nipinlẹ Ek... KAA SIWAJU
Mi o bawọn ta ilẹ ilu ri latigba ti mo ti wa lori itẹ- Olu Itori IROYIN OJUTOLE February 25, 2025 Olu tiuu Itori, Ọba Abdul-Fatai Akorede Akamọ, ti sọ pe oun ko bawọn ta pilọọti ilẹ to kere, depodepo pe oun yoo ta nla niluu ... KAA SIWAJU
Wọn fẹẹ fọrọ Afọbajẹ da wahala silẹ nilu Ketu-Ẹpẹ, Ọlọrun lo tu aṣiri wọn- Ọmọọba Adekọya Adefowora IROYIN OJUTOLE February 09, 2025 Ọmọọba Adekọya Babajide Adefowora, ti sọ pe bi ki i ba ṣe pe Ọlọrun ti aṣiiri obinrin ti wọn pe orukọ ẹ ni Tọpẹ, to gbidanwo lat... KAA SIWAJU
EGBE BEBE AANU FUN ORIYOMI HAMZAT IROYIN OJUTOLE January 11, 2025 Awon Omo egbe alatileyin fun gbajugbaja gbaja sorosoro ori radio nni, Alhaji ORIYOMI Hamzat lati orile ede America ati Canada t... KAA SIWAJU
Saheed Arẹgbẹsọla la n fẹ nipo ọba Isọlọ-Oloye Taorid Farounbi Alado IROYIN OJUTOLE January 10, 2025 Olori ẹbi Papa Alagbẹji, niluu Isọlọ, nipinlẹ Eko, Oloye Taorid Farounbi ti gbogbo aye mọ si Alado ti rọ gomina ipinlẹ Eko, Ọgbẹ... KAA SIWAJU
GBAJUGBAJA ONiROYIN, OLAIDE GOLD DI IYA IROYIN ILU MEIRAN, NIPINLE EKO IROYIN OJUTOLE January 07, 2025 Olaide Aderonke Gold ti gbogbo Ololufe e mo si Olaide Gold di IYA IROYIN fun ilu Meiran ni tile toko ati agbegbe e. Yiniyini ki ... KAA SIWAJU
Prophecy for 2025: A Year of Vengeance, Harvest, and Divine Shifts By Pro. Kingsley Aitafo IROYIN OJUTOLE December 21, 2024 Prophet Kingsley Aitafo, under the grace and spiritual leadership of His Eminence Rev. Pastor Samuel Belehou Oshoffa, founder of... KAA SIWAJU
Ijọ Cherubim ati Seraphim Society pe Ọgọrun-un ọdun. bẹẹni wọn ṣe iranti iku oludasilẹ ijọ wọn to papoda lọgbọn ọdun sẹyin IROYIN OJUTOLE December 21, 2024 KAA SIWAJU
Ojiṣẹ lṣẹdalẹ ṣatupalẹ ewi Wọle Ṣoyinka, Abiku si ede Yoruba. IROYIN OJUTOLE October 14, 2024 Ọgbẹni Olubunmi Olukanni, tawọn kan tun pe ni Ojiṣẹ Iṣẹdalẹ, to fi orileede Amerika, ni California, ti tun ewi kan ti Ọjọgbọn Wọ... KAA SIWAJU